We Are The Charleans

International News - A Yoruba Perspective

From BBC


Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin gba ìlànà lílo ẹ̀rọ àti fífi ẹnu kéde èsì ìdìbò lẹ́yìn ìfẹ̀hónúhàn ọmọ Naijiria
Awọn ẹgbẹ alatako atawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹsun kan ile igbimọ aṣofin agba wi pe wọn o fẹ ki eto ijọba awarawa dagba pẹlu bi wọn fagile lilo ẹrọ kọmputa fun akojọpọ ati ikede esi idibo lẹsẹ kẹsẹ ni Naijiria.

Alága àjọ Hajji, Abdullahi Saleh Usman, kọ̀wé fipò sílẹ̀
Ọpọ iroyin lo jade lọjọ Aje pe Usman kọwe fipo rẹ silẹ nitori ọpọ ẹsun ti wọn fi kan.

Bí a ṣe máa kojú ìṣòro ààbò - Kókó ohun tí Tinubu sọ níbi àpérò ìgbìmọ̀ alásẹ
Ààrẹ sọ àrídájú rẹ̀ fáwọn ọmọ Nàìjíríà pé ìṣèjọba òun ń sa gbogbo ipá láti ri pé ètò ààbò tó péye padà sípò ní gbogbo àwọn agbègbè tí ètò ààbò ti mẹ́hẹ.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Wọ́n rí òkú akọrin ẹ̀mí àtàwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ mẹta nínú 'studio' kan l'Eko, ọlọ́pàá mú afurasí kan
Akọrin ẹmi naa, Matthew Ogundele atawọn mẹta mii, Itunu Ogundele, Joseph Sanya, ati akọroyin ori ayelujara kan, Matthew Awosanya, tawọn eeyan mọ si JoesTv ni wọn ṣadeede ri oku wọn ninu yara ti wọn n lo fun orin kikọ to wa ni ile HFP Shopping Complex ni Abraham Adesanya ni Ajah.

Wo àwọn ọjà tí ìjọba Eko tìpa nítorí ìdọ̀tí
Ọpọ igba ni ijọba Eko maa n kilọ iwa idọti naa fun awọn olugbe agbegbe ati ọja pẹlu awọn olokowo adani, nipa lilo abala ofin imọtoto ti ọdun 2017 to koro oju si dida idọti lọna aitọ.

Ìjọba Kogi ti ọjà àti ibùdọ́kọ̀ pa láti lé agbébọn jáde
Atẹjade ti Kọmiṣanna fun iroyin nipinlẹ Kogi, Kingsley Fanwo, fi lede lanaa ọjọ kẹjọ, oṣu Keji ọdun 2026 yii lo kede bẹẹ.

Ọmọ mi méjì, ọmọ ìyáálé mi kan ni Amọtẹkun pa ni Akinlalu l'Osun, ìdájọ́ òdodo ni mo fẹ́ - Arábìnrin Oyebamiji
Arabinrin Alaba ni ọmọkunrin oun akọkọ Oyebamiji Ismail ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn de lati oko pẹlu baba rẹ nigba tawọn ẹṣọ Amotekun gbe ọkọ mẹta ati alupupu mẹfa de ti wọn si pa a.

Èèwọ̀ ni fún ẹnikẹ́ni láti daran jẹko ní ìta gbangba nílẹ̀ Ibadan - Olubadan
Olubadan ṣèkìlọ̀ fáwọn darandaran káàkiri ìpínlẹ̀ náà láti jáwọ́ nínú dída ẹran jẹko ní ìta gbangba tí wọn kò bá fẹ́ kojú ìgbẹ́jọ́ ilé ẹjọ́.

Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin gba ìlànà lílo ẹ̀rọ àti fífi ẹnu kéde èsì ìdìbò lẹ́yìn ìfẹ̀hónúhàn ọmọ Naijiria
Awọn ẹgbẹ alatako atawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹsun kan ile igbimọ aṣofin agba wi pe wọn o fẹ ki eto ijọba awarawa dagba pẹlu bi wọn fagile lilo ẹrọ kọmputa fun akojọpọ ati ikede esi idibo lẹsẹ kẹsẹ ni Naijiria.

Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera JOHESU padà sẹ́nu iṣẹ́ lẹ́yìn tí wọ́n ti gúnlè ìyanṣẹ́lódì fún bíi oṣù mẹ́ta
Ẹgbẹ oṣiṣẹ JOHESU pinnu lati pada sẹnu isẹ nibi ipade igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ naa to waye niluu Abuja lọjọ Ẹti ọsẹ to kọja.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ìdí ti ayẹyẹ ọjọ́ ìbí mi fi wáyé bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọjọ́ náà ni ìyá mi jáde láyé rèé- Fathia Williams
Williams kede eyi lẹyin wakati diẹ ti o ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi, ọdun marindinlọgọta niluu Eko.

Àwọn ajínigbé tó jí dókítà gbé l'Edo ṣìrìn, wọ́n fi ẹsẹ̀ ara wọn rìn wọnú àhámọ́ òfin
Tẹ o ba gbagbe, oṣu to kọja yii ni iroyin gbode, pe awọn ajinigbe ji Dokita kan, Abu Babatunde, gbe ni Auchi, ipinlẹ Edo .

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ìyá onílé tí wọ́n ló fún ọmọ ayálégbé rẹ̀ ní májèlé mu l'Ondo
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Abayomi Jimoh, ṣalaye pe iṣẹlẹ yii waye lọjọ kẹrin, osu Keji ọdun 2026, lagbegbe Omifon, nijọba ibilẹ Odigbo, ipinlẹ Ondo.

Ń kò padà sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, ipò gómìnà ìpínlẹ́ Ogun ni ojú mi wá - Iyabo Obasanjo
Kọmisana fun eto ilera nigba kan ri nipinlẹ Ogun ni ipadabọ rẹ sinu oṣelu lo da lori ipe lati ọdọ awọn ololufẹ rẹ ti wọn kesi pe ko ma pada bọ.

Fulani mẹ́ta tó wà ní àhámọ́ àwọn aṣọ́gbó nílùú Oloka l'Ogbomoso la fẹ́ dá sílẹ̀ ló jẹ́ ka ṣekúpa aṣọ́gbó márùn ùn - Afurasí jẹ́wọ́
Afurasi Abdullahi Abubakar ni Mohammed Dangi to jẹ igbakeji olori ẹgbẹ janduku agbebọn ọhun lo pe oun wi pe kawọn jọ ṣiṣẹ naa.

Ìjàmbá ọkọ̀ gba ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ KWASU tó fẹ́ ṣe ìdánwò àṣekágbá
Oloogbe naa fẹ se asakagba idanwo rẹ ni ile ẹkọ naa nigba to jade laye.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Àràmàndà Odò Ado Awaye l'Oyo, àdágún omi órí àpáta tí kò kún rí tí kò sì lọọlẹ̀ rí
Iru odo yii meji lo wa lagbaaye, ọkan ni Colorado ni orilẹ-ede Amerika ati ikeji ni odo Adagun Ado Awaye nipinlẹ Oyo lorilẹ-ede Naijiria.

Mọ̀ nípa àṣẹ tuntun tí ilé ẹjọ́ pa lórí àyẹ̀wò DNA fún Liam ọmọ Mohbad
Ilẹ ẹjọ pàṣẹ tuntun yii lẹyìn ede-aiyede to ṣẹlẹ laarin ẹbi Mohbad ati Wunmi to jẹ opo rẹ lori ọrọ ayẹwo DNA fún Liam.

A ti sin òkú Aunty Ajara, ẹ má dá owó fún ẹnìkankan mọ́- Ridwan Lasisi
Oṣere ẹgbẹ rẹ miran, Kudirat Shoremi (Mama no network), fidi iku naa mulẹ fun BBC News Yoruba laaarọ oni.

Ṣé lóòótọ́ ni àwọn ṣọ́jà America mú Sheikh Gumi ní pápákọ̀ òfurufú?
Papakọ ofurufu kan ni aworan naa ṣafihan, pẹlu Sheikh Gumi ti awọn ṣọja oyinbo ko ni papamọra.

Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria, ẹ jẹ́ káwọn Amotekun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ padà l'Osun láti lè dènà irú ikọlù tó ṣẹlẹ̀ ní Kwara - Adeleke
Gomina Adeleke to fidi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ, Olawale Rasheed, fi sita, ṣalaye pe ofin ti ileeṣẹ ọlọpaa fi de awọn Amotekun lo jẹ ki iṣẹlẹ ijinigbe to waye lagbegbe Ore Igbomina laipẹ yii waye.

Wo irúfẹ́ àwọn èèyàn tí ìjọba Saudi Arabia ti fàyè gbà láti maa ra ọtí mu báyìí
Labẹ ofin to bi bẹrẹ si ni ṣiṣẹ lati ipari ọdun 2025 bayii, awọn ọlọrọ ti kii ṣe musulumi ti lanfaani lati maa ra ọti nibi ti wọn ti n ta a bayii.

Ṣé lóòótọ́ ni Amẹrika ń sọ̀rọ̀ lórí pínpín Naijiria nítorí ìṣekúpani àwọn Kristẹni? Àlàyé rèé
Aṣofin Riley Moore sọ pe pinpin orilẹede Naijiria ko saba jẹyọ ninu gbogbo ijiroro atawọn ipade toun ṣe ni Naijiria.

Ibá Lassa fojú hàn ní ìpínlẹ̀ Plateau, ó ti mú ẹ̀mí mẹ́rin lọ
Kọmisana fun eto ilera nipinlẹ Plateau, Dokita Nicholas Baamlong, lo kede eyi nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lọjọ Ṣatide ni ọfisi rẹ ni Jos, nibi to si ṣalaye ni kikun ati igbesẹ ti ijọba n gbe lori itankalẹ aisan Lassa naa

Èèmọ̀! Ọ̀ọ̀nì ṣekúpa ọkùnrin kan tó sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀ lọ́wọ́ erin lákátabú
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Zambia ṣalaye Ọgbẹni Dean Nyirenda n bọ pẹlu ọrẹ rẹ meji lati ibi ti wọn ti lọ pẹja lỌjọru ọsẹ to kọja nigba ti wọn sadeedee pade awọn erin lọna.

Ṣé lóòótọ́ ni wọ́n yìnbọn pa ọmọ Gaddafi, Saif al-Islam? Ohun tí a mọ̀ rèé
Agbẹjọro rẹ sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe igbimọ ẹlẹni mẹrin lo ṣekupa oloogbe ni ile rẹ to wa ni ilu Zintan, bo ti lẹ jẹ pe wọn ko ti fidi eeyan to wa lẹyin ikọlu naa mulẹ.

Kí ni èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí owó táwọn abániwálé máa ń fi kún owó ilé?
BBC News Yorùbá bí àwọn ọmọ Nàìjíríà láti sọ àríwisí wọn lórí owó táwọn abániwálé máa ń fi si owo ilé.

Ìjọba Kogi ti ọjà àti ibùdọ́kọ̀ pa láti lé agbébọn jáde
Atẹjade ti Kọmiṣanna fun iroyin nipinlẹ Kogi, Kingsley Fanwo, fi lede lanaa ọjọ kẹjọ, oṣu Keji ọdun 2026 yii lo kede bẹẹ.

A ti fi ikọ ológun tí yóò kún Naijiria lọ́wọ́ láti ṣẹ́gun agbésùnmọ̀mí ránṣẹ́- Ológun America
Ọga ologun oju ofurufu, Dagvin R. M. Anderson to n ri si ọrọ ilẹ Africa l'America; 'U.S. Africa Command' (AFRICOM), lo fidi eyi mulẹ lọjọ Iṣẹgun ana.

Akẹ́kọ̀ọ́ Fáṣítì méjì dèrò ọrùn lẹ́yìn ayẹyẹ ìgbaniwọlé nílé ìtura l'Ondo
Ajọyọ igbaniwọle naa ni wọn lọ ṣe nile itura kan, nibẹ ni wọn ni wọn ti wẹ ninu adágún omi (swimming pool). Iwẹ naa lo pada gba ẹmi lẹnu wọn bi iroyin ṣe wi.

Àwọn òṣìṣẹ́ fẹ̀yìntì ìpínlẹ̀ Ọyọ fi ẹṣin funfun ta Gómìnà Makinde lọ́rẹ
‎‎Abatan ṣalaye wi pe ẹgbẹ naa pinnu lati fun Gomina Seyi Makinde ni ẹṣin funfun nitori awọn itumo to rọ mo.

Ọdún ìbílẹ̀ àwọn Ohori Ije wáyé ní Benin, Gẹ̀lẹ̀dẹ́ àti Ponsere gbòde
Yatọ si awọn ijo ibilẹ, awọn to fi ọ̀be dara nipa ṣiṣa ara wọn lọbẹ ko gbẹyin pẹlu.

Ọ̀kadà tí wọn gbé wa tó 80, wọ́n tò ní méjì, mẹ́ta sórí ọ̀kadà kọọkan, wọ́n mura bii ológun- Emir Kaiama
BBC News Yoruba sabẹwo si ilu Kaiama, Woro ati Nuku lati mọ ohun ti o fa ikọlu yii ati iye awọn eniyan to ba ikọlu naa lọ ni pato.

Gbogbo àwọn olùjọ́sìn táwọn agbébọn jí gbé ní Kaduna gba ìtúsílẹ̀
Ileeṣẹ ọlọpaa ni lati ọjọ ti wọn ti jawọn olujọsin naa gbe ni wọn ti moribo lasiko tawọn ajinigbe naa n gbe wọn kaakiri.

Àwọn ajínigbé gba mílíọ̀nù méjìlá náírà, power bank méjì láti tú Ọba Olanipekun tí wọ́n jí gbé ní Kwara sílẹ̀
Ni ọjọ Kẹrinlelogun oṣu Kejila, ọdun 2025 ni awọn ajinigbe naa ji Kabiyesi ati ọmọ rẹ, Olaolu to jẹ agunbanirọ gbe, ti wọn si yinbọn ba olori.

Ìtàn tó rọ̀ mọ́ orúkọ Kòbọmọjẹ́ ní Ibadan àti ìdí tí àṣà dídá abẹ́ f'ọmọbìnrin ṣe dohun ìgbàgbé ní agboolé náà
Ọ̀pọ̀ ìdílé ni wọ́n yan iṣẹ́ abẹ dídá láàyò láyé àtijọ́ gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ àmọ́ lóde òní àṣà yìí ti ń di ohun ìgbàgbé nítorí àwọn ewu tó rọ̀ mọ́.

Atiku, Bode George, ẹgbẹ oṣelu PDP, LP atawọn mii koro oju sawọn sẹnẹtọ lori atunṣe ofin idibo
Igbesẹ naa fa awuyewuye nitori fifi ẹrọ kọmputa gbe esi idibo sita ni ọpọ gbagbọ pe o le dena eeru ninu eto idibo gbogbogbo ọdun 2027.

Ìyàwó mẹ́wàá ni bàbá mi fẹ́, mó fẹ́ kọ ìyàwó mi sílẹ̀ báyìí kí n lè fẹ́ ìyàwó púpọ̀ - Kunle Afolayan
Nigba to n sọrọ lori fiimu rẹ to ṣẹṣẹ jade, 'Anikulapo,' Afolayan ṣalaye pe oun fẹ gbe igbesẹ yii tori lati idile oniyawo pupọ loun ti wa.

Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Eko fẹ́ ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn olórí agbègbè tí wọ́n wó ilé wọn ní Makoko
Ọla ode yii ti i ṣe ọjọ kẹta, oṣu Keji ọdun 2026 ni ipade naa yoo waye laaarin awọn olori agbegbe ti ile wiwo naa kan ati ijọba.





We always perform at our best when we work together

Our mission is to provide the means & technical know-how to accomplish the aforementioned with HUMILITAS - always



This Section Can Accommodate Your Adverts





Charleans In Celebration Mode

We have put an assorted mix of pics here for your enjoyment. We are always hungry for more - so if you have taken or have access to some pics remotely related to our issue, please do not hesitate to send them to the web admin team

SCOBA PARTNERS

corporates and enterprise businesses we have the pleasure to connect with.