O kere tan, awọn ẹṣọ eleto aabo bii ẹgbẹrun mẹẹdogun ni ajọ naa ti gba lati mojuto eto idibo naa, bakan naa si ni ajọ OYSIEC ti fi iroyin lede nipa igbanisiṣẹ awọn oṣiṣẹ eleto idibo bii ẹgbẹrun lọna ogoji ti yoo ṣe atọkun eto idibo naa jakejado ipinlẹ Ọyọ.
Dokita Carles Pedret, akọṣẹmọṣẹ lati ileewe to n ri si ilera nipa ere idaraya ni Yunifasiti Barcelona ni iṣan Soleus nilo lati maa ṣiṣẹ deede keeyan le wa lalaafia ara.
Atẹjade kan ti Kmisana feto iroyin nipinlẹ Eko fisita loju opo Twitter rẹ, ni ko si ohun to jọ afikun owo osu osisẹ, awọn araalu kan ṣi gomina naa gbọ ni.
Alaga igbimọ ẹlẹni meje to dari eto idibo naa nipinlẹ Ondo ti i ṣe Igbakeji Gomina Ipinlẹ Bayelsa, Sẹnẹtọ Ewhrudjakpo Oborawhartevwo lo kede Ajayi gẹgẹ bi ẹni to bori.
Igbimọ adajọ ẹlẹni meje ti adajọ Gertrude Torkonoo dari rẹ fidi rẹ mulẹ pe ipo aya aarẹ ati aya igbakeji aarẹ kii ṣe ipo ọfiisi ijọba to tọ si owo oṣu gbigba.
BBC Yorùbá bá Baba awo Obafemi Makinde sọ̀rọ̀ lórí Àtúpalẹ̀ ẹ̀sìn ifá, ẹni tó ṣàlàyé bí Orunmila ti ṣẹ̀ wá láti ilẹ̀ Egpty yàtọ̀ sí ilú Ile Ife tí ọ̀pọ̀ èèyàn rò pé ó jẹ́ Olùdáyé.
Iroyin ni ọkan lara awọn oṣiṣẹ SARS, ti ijọba fopin si lọdun meji sẹyin ni ọlọpaa to yinbọ naa, eyii to ṣekupa agunbanirọ ti wọn pe orukọ rẹ ni Iyanda Damilola.
BBC Yorùbá wà ní ìlú Oyo fún ìrántí Aláàfin Lamidi Olayiwola Adeyemi tó wàjà lọ́dún méjì sẹ́yìn láti fojú ṣe mẹ́rin àwọn ètò ìrántí fún ọba tó dí olóògbé náà.
We have put an assorted mix of pics here for your enjoyment. We are always hungry for more - so if you have taken or have
access to some pics remotely related to our issue, please do not hesitate to send them to the web admin team