We Are The Charleans

International News - A Yoruba Perspective

From BBC


Gbogbo nnkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìrìnàjò Muhammadu Buhari láti kékeré títí tó fi kú
Olori ijọba ologun nigba kan ri ọhun pada di oloṣelu, to si wọle sipo aarẹ lọdun 2025.

Ààrẹ Naijiria tẹ́lẹ̀, Muhammadu Buhari ti jáde l'áyé
Ọsan ọjọ Aiku, ọjọ kẹtala, oṣu Keje, ọdun 2025 ni oluranlọwọ pataki fun , Garba Shehu, fi ikede iku rẹ sita fun awọn akọroyin.

Afurasí agbésùnmọ̀mí Lakurawa ṣekúpa ọlọ́pàá mẹ́ta ní Kebbi, agbébọn 400 kojú ọmọ ogun
Oju ọna Tiili, to wa ni ijọba ibilẹ Bunza ni iṣẹlẹ ọhun ti waye lasiko ti wọn n gbiyanju lati ji awọn arinrinajo kan gbe nibẹ.

'Àwọn òbí mi rò pé mo ti jóná mọ́lé, láì mọ̀ pé ìbátan bàbá mi ló jí mi gbé fi ṣọmọ'
Delimar poora ninu ina to ṣẹyọ nile wọn lọdun 1997, amọ ṣe ni wọn ji i gbe.

Àwọn ànfààní tó wà nínú sísọ ọ̀rọ̀ ẹni lẹ́yìn tàbí gbéborùn ṣíṣe
Ko si awujọ naa ti ẹnikan ko ti ni i sọrọ nipa ẹnikeji rẹ lẹyin. O le jẹ nipa iwa ti ẹni ti wọn n sọrọ rẹ lẹyin naa ni lọwọ, tabi iru aṣọ to maa n wọ, iru ile to ti wa ati bẹẹ bẹẹ lọ.

Mo ṣetán láti gbọ́ àwíjàre àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Poly Ibadan tó ń ṣèwọ́dé lórí ayípadà orúkọ ilé ẹ̀kọ́ náà - Makinde
Loṣu Kẹfa to kọja ni Makinde fi orukọ gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri, Ọmọwe Omololu Olunloyo sọ orukọ ile ẹko naa eyi ti ọgọọrọ awọn akẹkọọ ti n ṣe iwọde tako.

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ ìpínlẹ̀ Eko àti ìdí tó fi ṣe pàtàkì
BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀ ní Eko tí yóò wáyé lọ́la ọjọ́ Àbámẹ́ta, ọjọ́ Kejìlá, oṣù Keje, ọdún 2025.

Ilé ẹjọ́ ní nọ́ọ̀sì tó fún Mohbad lábẹ́rẹ́ gbọdọ̀ jẹ́jọ́, bu ẹnu àtẹ́ lu Wumi àti bàbá olóògbé
Ọjọ kejila, oṣu Kẹsan an, ọdun 2023 ni Mohba jade layẹ lẹyin to gba itọju ninu ile latari bo ṣe ṣeṣe nibi ode kan.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Wo ohun tó n ṣẹlẹ̀ sí ọkàn rẹ bí o bá sá eré ìje olóbìírípo láì sinmi
Ere sisa yii ju ki eeyan sare onikilomita mejilelogoji (42km )lọ, iyẹn maili mẹrindinlọgbọn (26miles).

Ìlú kan rèé ní Nàíjíríà níbi tí èèyàn àti ẹranko tí ń pín omi odò mu torí ọ̀dá omi
BBC de Ilu Dutsen Bakoshi, abule kan ni ijọba ibilẹ Shanono nipinlẹ Kano, nibi ti wọn ti n koju ipenija omi lati dana tabi fun mimu, paapa lasiko ẹru.

Peter Obi ṣàlàyé onírúurú ọ̀nà tí yóò gbà mú àyípadà bá Nàíjíría
Peter Obi sọ èyí nígbà tó kópa níbi ètò kan, tó sì ní ó yẹ kí ẹnikẹ́ni tó bá jẹ́ ààrẹ ṣetán láti fi ẹ̀mí ara rẹ̀ lélẹ̀ nígbà tí ẹ̀mí àwọn èèyàn rẹ̀ bá wà nínú ewu.

Ìwádìí ìjìnlẹ̀ rèé nípa Ìjàpá, bó ṣe ń ní ìmọ̀lára àyíká rẹ̀, bó ṣe ń dunnú tàbí gbèrò ohun rere bí èèyàn
Ọjọgbọn Oliver Burnman, onimọ nipa iṣesi ẹranko ati alaafia wọn, sọ nipa abọ iwadii to ni yoo mu iyatọ wa nipa imọ nipa awọn ẹranko afayafa daadaa.

Àlàyé rèé lórí bí orí ṣe kó igbákejì ààrẹ yọ, tí wọn kò fi yọ́ kúrò lásìkò tó wà nípò gómìnà
Kassim Shettima salaye ọrọ yii nibi ifilọlẹ iwe kan ti minisita tẹlẹ fun eto idajọ, Mohammed Bello Adoke gbe kalẹ, eyi to waye ni Abuja.

Àwọn wo ló ń dúnkokò mọ́ Iyabo Ojo tó ṣe ń lọgun pé inú ewu ni òun àti ìdílé òun wà, wọ́n fẹ́ gbẹ̀mí òun ?
Nínú àtẹ̀jáde kan tí Iyabo Ojo fi sí ìkànnì Instagram rẹ̀ lọ́jọ́bọ̀, ọjọ́ Kẹwàá, oṣù Keje, ọdún 2025 ló ti ṣàlàyé àwọn nǹkan tó ti ń là kójá lẹ́nu ọjọ́ mẹ́ta báyìí, tó sì ní pé àwọn kan ń mọ̀ọ́mọ̀ ṣe ìkọlù sí òun.

Kí ló dé tí Naíjíríà yarí láti gba ọ̀pọ̀ àtìpó ọmọ ilẹ̀ Venezuela tí Trump fẹ́ fi ránṣẹ́?
Minisita fun ọrọ ilẹ okeere, Yusuf Tuggar ni Naijiria gan ni ọpọ iṣoro lati dojukọ ni ikapa rẹ, ti ko si le jẹ orilẹede kẹta fun awọn ẹlẹwọn lati oke okun.

"Ogún ọdún rèé tí mo ti ń ta ẹ̀pà, gúgúrú àti dáńkúà fáwọn olólùfẹ̀ẹ́ bọ́ọ́lù Kwara United, kò sí ìlú tí ń kìí tẹ̀lé wọn lọ"
BBC Yorùbá ṣe alábàápàdé obìnrin kan, Oluwatoyin Abdullahi tó ń ta ẹ̀pà lẹ́yìn àwọn olólùfẹ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Kwara United, tó sì ń tẹ̀lé wọn kiri ilẹ̀ Yorùbá.

Wo ààrùn márùn-ún tí èèyàn le kó látara ìbálòpọ̀ àti ìtọ́jú wọn
Àwọn ààrùn yìí, èyí tó máa ń wáyé nípa ìbálòpọ̀ tó fi mọ́ ojú ara obìnrin, ojú ìdí tàbí ìbálòpọ̀ láti ẹnu le fa ìpèníjà ìlera tó lágbára.

Kí ni Cryptocurrency, tí EFCC ń kígbe pé àwọn olóṣèlú kan ń lò láti kó owó ìlú lọ sókè òkun?
Bí EFCC ṣe ń kígbe pé àwọn olóṣèlú kan ń lò Cryptocurrency láti kó owó ìlú lọ sókè òkun, BBC News Yorùbá ṣe àtúpalẹ̀ ohun tí Crypto jẹ́ àti bí wọn ṣe le lò ó láti kó owó pamọ́.

Ṣé lóòótọ́ ni ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún ọkùnrin kan fẹ́sùn pé ó ra jẹnẹrétọ̀ tí wọ́n jí gbé? Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun ṣàlàyé
Ṣáájú ni ìròyìn Ogbonna gbá orí ayélujára lẹ́yìn tó rí ìtúsílẹ̀ kúrò lọ́gbà ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn ọdún méjìlélógún pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Abia, Alex Otti.

Moji Afolayan: Ọ̀pọ̀ àwọn alágbàtà fíìmù ló máa ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ obìnrin, kí wọ́n tó lò wọ́n nínú eré láti di olókìkí
Láti bíi ọdún díẹ̀ sẹ́yìn ni Moji Afolayan kó ti sábà kópa nínú eré mọ́ kó tó di pé ó kópa nínú Anikulapo tí Kunle Afolayan ṣe.

Akẹ́kọ̀ọ́ tó gba máàkì 375 rugi oyin, àjọ Jamb ṣàlàyé ìdí tí kò lè fi rí fásitì wọ̀ àti ojúṣe àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lásìkò ìdánwò
Agbẹnusọ JAMB atri onimọ nipa eto ẹkọ tu pẹrẹpẹrẹ ojuṣe awọn akẹkọọ lasiko idanwo JAMB.

Afurasí aláboyún akẹ́kọ̀ọ́bìnrin fásítì UNIPORT dáná sun ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀, ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
Ibatan ọrẹbinrin naa sọ fun BBC pe iṣẹlẹ ọhun waye lopopona Ogbogoro ni Choba lagbegbe ọgba ile ẹkọ fasiti UNIPORT.

Ikú ń rọ̀ dẹ̀dẹ̀ lórí alárùn HIV/AIDS bíi 400m, èèyàn 6m tuntun le kó àrùn náà torí ìrànwọ́ Amẹ́ríkà tó dúró
Ni South Africa, eeyan to to 7.7 million lo n gbele aye pẹlu arun HIV, eyi lo si pọ ju lagbaaye, gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ UNAIDS.

Kí ló dé tí Bello Turji, ògbóǹtagí agbébọn tó ń da ẹkùn àríwá láàmú, ṣe fẹ́ parí ìjà pẹ̀lú ìjọba?
Èyí ló ń wáyé lẹ́yìn tí iléeṣẹ́ ológun Nàijíríà sọ pé ìwà ìgbéṣùmọ̀mí ń peléke si, tí wọ́n sì kéde láìpẹ́ yìí pé àwọn ti ṣekúpa èèyàn kan tó ń ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú Turji, Kachalla Yellow Danbokolo.

Wo iye máàkì tí akẹ́kọ̀ọ́ fi ń wọlé sí fásitì ní ọdún márùn-ún sẹ́yìn àti ìdí tí JAMB fi kéde 150, bíi gbèdéke máàkì láti wọlé sí fásítì ní 2025
JAMB ṣe ikede gbedeke maaki lati wọle si fasiti lẹyin ipade wọn ni Abuja pẹlu awọn ọga agba awọn ile ẹkọ fasiti atawọn ile ẹkọ giga mii ni Naijiria.

Ìjọba àpapọ̀ fèsì lẹ́yìn tí Amẹríkà fún okùn físà gbígbà mọ́ ọmọ Naijiria lọ́rùn
Lẹyin ikede ọhun ni ileeṣẹ to n ri si ọrọ ilẹ okeere ni Naijiria naa fi atẹjade tirẹ sita lati rọ Amẹrika pe ko yi igbesẹ naa pada.

Èyí ni iye àkàsọ̀ tí Oludije sípò Olubadan yóò gun, kò tó dé orí ìtẹ́
Bi eeyan yoo ba de ipo ọba Ibadan ti i ṣe Olubadan, o kere tan, ẹni naa yoo gun akasọ mejilelogun tabi mẹtalelogun ko too de ipo ọba Ibadan.

Kí ló dé táwọn Olubadan ń wàjà léraléra àti ìdí tí Ibadan ṣe ń jẹ́ Ọmọ Agbọ́tikúyọ̀?
BBC Yoruba kan si ọkan lara awọn Oloye ilẹ Ibadan, Agba oye Lekan Alabi, to tun jẹ Maye Olubadan, lati tan imọlẹ si ibeere mejeeji yii.

Ìtàn tó rọ̀ mọ́ orúkọ Kòbọmọjẹ́ ní Ibadan àti ìdí tí àṣà dídá abẹ́ f'ọmọbìnrin ṣe dohun ìgbàgbé ní agboolé náà
Ọ̀pọ̀ ìdílé ni wọ́n yan iṣẹ́ abẹ dídá láàyò láyé àtijọ́ gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ àmọ́ lóde òní àṣà yìí ti ń di ohun ìgbàgbé nítorí àwọn ewu tó rọ̀ mọ́.

Rasheed Ladoja: Akọni olóṣèlú tó fi sùúrù gba adé Sẹ́nátọ̀ àti gómìnà, tó tún fẹ́ gba adé Olubadan kẹrìnlélógójì
BBC Yoruba se akojọpọ itan igbe aye agba oye Rasheed Adewolu Ladoja eyi to yẹ ki ọpọ araalu mọ.





We always perform at our best when we work together

Our mission is to provide the means & technical know-how to accomplish the aforementioned with HUMILITAS - always



This Section Can Accommodate Your Adverts





Charleans In Celebration Mode

We have put an assorted mix of pics here for your enjoyment. We are always hungry for more - so if you have taken or have access to some pics remotely related to our issue, please do not hesitate to send them to the web admin team

SCOBA PARTNERS

corporates and enterprise businesses we have the pleasure to connect with.