Àwọn aṣòfin mẹ́rindínlọ́gbọ̀n ni wọ́n ń fẹ̀sùn kan gómìnà àti igbákejì rẹ̀ ọ̀hún nínú ìwé àkọránṣẹ́ kan tí wọ́n fi ṣọwọ́ sí olórí ilé aṣòfin, Martin Amaewhule lọ́jọ́ Ajé.
Abọ iwadii ajọ kan, Observatory for Religious Freedom in Africa,sọ pe ida aadọrun-un (90%) awon Kristẹni ti wọn n pa kaakiri agbaye lọdun jẹ ọmọ Naijiria.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ẹnu ọjọ mẹta yii ni Ijoba Lande bẹrẹ si n milẹ titi lori ayelujara lẹyin to fẹsun kan iyawo rẹ pe o ba ọkunrin mọkanlelogun ni ibalopọ.
Àtẹ̀jáde ti agbẹnusọ ọlọ́pàá Ogun, Omolola Odutola fi léde ní Ajele Oloyede jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọlọ́pàá tó ń pèsè ààbò fún iléeṣẹ́ kan tó wà ní Igbesa, ìpínlẹ̀ Ogun.
Ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle, The Punch, Jamiu ni asiko fun iwadii nipa iku baba wọn ti kọja, ti ọpọ awọn eeyan to mọ nipa ohun to waye ni ọjọ Kejila oṣu Kẹfa ti jade laye.
BBC Yorùbá bá gómìnà ìpínlẹ̀ Osun, Ademola Adeleke sọ̀rọ̀, tó sọ ọ̀pọ̀ aṣeyọrí rẹ̀ áàrin ọdún mẹ́ta, àwọn tó ń darí ìjọba Osun, ọ̀rọ̀ bàbá ìsàlẹ̀, ipò ìlera àti bó ṣe máa ń jó.
Ẹrọ "drone" ni ijọba naa fi n ṣọ awọn obinrin ti ko ba lo hijab, bẹẹ ni wọn tun gbe aapu kan kalẹ ti araalu le maa lo lati fi ọrọ awọn obinrin to ba kọ lati lo hijab to ijọba leti.
Lapapọ, atunṣe mọkandinlogun (19) lo ni o waye, titi de ori eyi ti awọn gomina kan lawọn ko fẹ ko ri bẹẹ lapa Ariwa, ṣugbọn ti Aarẹ Tinubu sọ pe ilana to daa ju niyẹn.
Lẹ́yìn tí Peter Obi ti fìdí rẹmi sọ́wọ́ ààrẹ Bola Ahmed Tinubu níbi ètò ìdìbò ọdún 2023 níbi tó ti gbé ipò kẹta, Peter Obi kò sinmi láti máa ṣe àbẹ̀wò sáwọn èèkàn olóṣèlú káàkiri Nàìjíríà.
Lábẹ́ ìwé òfin ìwà ọ̀daràn Nàìjíríà, ìwà ìpànìyàn, ìgbéṣùmọ̀mí, ìdigunjalè, ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ fún ìpànìyàn lọ́nà àìtọ́, ìdìtẹ̀gbàjọba jẹ́ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí ilé ẹjọ́ fi le gbé ìdájọ́ ikú kalẹ̀ fún ọ̀daràn.
We have put an assorted mix of pics here for your enjoyment. We are always hungry for more - so if you have taken or have
access to some pics remotely related to our issue, please do not hesitate to send them to the web admin team