It is within us to build this fraternity network so that others can see how we have utilised all that wonderful upbringing and so much more inculcated at St.Charles
Lọsẹ to kọja ni Sheikh Ayilara fi oye Asiwaju/Baba Isale Adini ilẹ Ogbomoso da Sẹnẹtọ Adeseun to ṣoju ẹkun aarin gbungbun Oyo laarin ọdun 2011 si 2015 nile aṣofin agba l'Abuja lọla.
Aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ, (NLC) lorilẹede yii; Kọmureedi Joe Ajaero ati Festus Osifo(TUC), koro oju si ijọba Naijiria, pẹlu alaye pe ko yẹ ki oṣiṣẹ tun di atọrọjẹ lẹyin iṣẹ ti wọn n ṣe.
Ajọ International Organization for Migration (IOM) pẹlu ajọṣepọ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri, 'National Emergency Management Agency' (NEMA), ni wọn ko wọn wale pẹlu awọn alẹnulọrọ mi-in.
Ẹ̀sùn pé ó ṣe owó ilẹ̀ òkèèrè lọ́nà àìtọ́ ni gbajúmọ̀ náà ń kojú, bí wọ́n ṣe fẹ̀sùn kàn-án pé ó ná owó dọ́là ilẹ̀ Amẹ́ríkà lọ́nà àìtọ́ èyí tí wọ́n ní ó lòdì sí òfin Foreign Exchange Act.
Ọsan ọjọ akọkọ tiwọn ba wọ inu ipade idakọnkọ naa ni wọn yoo di ipele akọkọ idibo naa. Amọ, yoo to igba mẹrin ọtọọtọ ti wọn yoo maa dibo lojoojumọ lẹyin eyi.
A gbọ pe pupọ ninu awọn ẹni ti ọlọpaa doola naa lo jẹ ọmọ orilẹede Democratic Republic of Congo ti wọn tan wa si Naijiria pẹlu ẹtan pe wọn yoo fun wọn ni iṣẹ.
Lasiko ti awọn eeyan ilu naa n ṣe ọfọ eeyan kan ti wọn ṣẹṣẹ sin oku rẹ tan lawọn agbebọn naa ṣina ibọn bo awọn eeyan ti wọn si pa awọn meje ti wọn pa ni Koful.
Gẹgẹ bawọn onpitan ṣe wi, poopu mẹta lo ti jẹ ri ti wọn ti orirun wọn jẹ ti Africa, eyi to sunmọ ju ninu wọn ni wọn ni iku rẹ ti le ni ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta (1,500 years ago.)
Ninu atẹjade kan ti Gomina Sanwo-Olu fi sita lọjọ Aiku lo ti ni Peter Obi ko yẹ lẹni to yẹ ko maa sọrọ abuku si aarẹ to n ṣelu lọwọ, ati awọn olori to ti kọja.